Загрузка страницы

Exclusive! Popular Prophet reveals what God said about Yoruba Nation

O sele! Wolii Wale Olagunju, gbajumo Wolii ariran so ohun t'Oluwa so nipa idasile orile-ede Oduduwa
*O so nnkan ti yoo sele ki osu kejila too de
*O tun so asotele nla nipa Sunday Igboho, Tinubu ati Seyi Makinde

Gbajumo Wolii ariran ilu Ibadan n'ipinle Oyo nni, to tun je Wolii ti ki i we (bath), iyen Wolii Wale Olagunju ti so ohun t'Oluwa so nipa ijangbara fun idasile orile-ede Oduduwa pelu ohun ti yoo sele ki osu kejila odun yii too de.
E gbo, kin ni Oluwa so nipa "Yoruba Nation"? Ki lo fee sele ninu osu kejila odun yii? Asotele nla wo ni Wolii Olagunju so nipa Oloye Sunday Igboho, Gomina Seyi Makinde ipinle Oyo ati Asiwaju Bola Tinubu?

Видео Exclusive! Popular Prophet reveals what God said about Yoruba Nation канала DIVINE SEED OF GOD CHAPEL MINISTRY
Показать
Комментарии отсутствуют
Введите заголовок:

Введите адрес ссылки:

Введите адрес видео с YouTube:

Зарегистрируйтесь или войдите с
Информация о видео
30 августа 2021 г. 21:34:23
00:03:37
Яндекс.Метрика